Ìpínlẹ̀ Èkó jẹ́ ìpínlẹ̀ kan ní gúúsù ìwọ̀-oòrùnNàìjíríà láàárin àwọn ìpínlẹ̀ mẹ́rìndínlógójì náà, ó pọ̀ níye ó sì kéré ní ààyè. Ó sopọ̀ mọ́ gúúsù nípasẹ̀ àwọnìgbèríko Benin àti sí ìwọ̀-oòrùn nípasẹ̀ ààlà òkèèrè pẹ̀luÌlu Benin, Ìpínlẹ̀ Èkó ń pín àwọn ààlà pẹ̀lúÌpínlẹ̀ Ogun sí ìlà-oòrùn àti àríwá ní èyí tí ó mu jé ìpńilẹ̀ kan ṣoṣo ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó pín ààlà pẹ̀lú ìpínlẹ̀ kan péré. Orúkọ fúnìlú Èkó — Ìlú tí ó pọ̀ jùlọ ní ilẹ̀ adúláwọ̀ — wọ́n dá ìpínlẹ̀ náà látara agbègbè Ìwọ̀ Oòrùn tí ó sì jẹ́ olú-ìlú tẹ́lèrí ní ọjọ́ kẹ́tadínlọ́gbọ̀n oṣù karùn-ún, ọdún 1967.[4][5]
Gégẹ́ bí ìtọ́ka agbègbè, Ìpínlẹ̀ Èkó jé ilẹ̀ omi tí ìdá-mẹ́rin rẹ̀ dín ní díẹ̀ kúnfún òṣà, itọ́ àti àwọn odò.[6] Èyí tí ó fẹ̀ jù nínú àwọn omi wọ̀nyí ni ọ̀sà Èkó àtiLekki nínú ìpínlẹ̀ náà pẹ̀lú odòOgun àtiOsun tí ó ń sàn wọnú wọn. Àwọn omi yòó kù jẹ́ itọ́ tí ó ń sàn kiri ìpínlẹ̀ náà tí wọ́n sì jẹ́ ọ̀nà ìrìnàjò pàtàkì fún àwọn èèyàn àti àwọn ọjà. Nítòsí etí omi, ìpínlẹ̀ yìí bákan náà ṣàkónú àwọn onírúnrú ohun ọ̀gbìn, ẹranko àti ẹranmi gẹ́gẹ́ bí ẹjá ṣe wà náà niàwọn ẹranmi ilẹ̀ adúláwọ̀ àti àwọnọ̀ọ̀nì.[7][8]
Ìpínlẹ̀ Èkó ti jé ibùgbé fún ọdún tó ti pẹ́ nípasẹ̀ àwon ọ̀wọ́ onírúnrú ẹ̀yà onílùú, nípàtàkì awọnọmọ Yoruba ni wọ́n ń gbé káàkiri ìpínlẹ̀ náà àmọ́ àwọn èèyanEwe àtiOgu náà ń gbé ibi tí o nasẹ̀ lápá ìwọ̀ oòrùn.
Gẹ́gẹ́ bí àbáyọrí síṣí lọ láti orílẹ̀ èdè kan sí òmíràn láti bíi ọ̀rúndún sẹ́yìn, ìpínlẹ̀ Èkó pẹ̀lú ti ní èrò tó pọ̀ tí wọn kìí ṣe àwọn ọ̀wọ́ ẹ̀yà orílẹ̀-èdè Nàìjíríà pẹ̀lúEdo,Fulani,Hausa,Igbo,Ijaw,Ibibio, àti èèyànNupe láàárin àwọn ọ̀wọ́ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà yòókù. Àwọn ọ̀wọ́ mìíràn wa látìta tí wọn wá láti àwọn ìlú tí ó pín ààlà orílẹ̀-èdè Nàìjíríà pèlúSaro (Sierra Leonean) àtiAmaro (Brazilian) gẹ́gẹ́ bí àwọn ọ̀wọ́ tí wọn ṣẹ̀ wá tí wọ́n kó lẹru tẹ́lẹ̀rị́ tí wọ́n padà sílẹ̀ adúláwọ̀ ní àwọn ọdún 1800 pẹ̀lú àwọn àwùjọ àárín ìlà-oòrùn orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí wọ́n ti wà ti pẹ́ (pàápàáSyrian àtiLebanese orílẹ̀-èdè Nàìjíríà)[9] pẹ̀lú di èrò ní apákan gbòógì ní ìpínlẹ̀ Èkó pẹ̀lú àwọn tí wọ́n ṣí wá láìpẹ́ látiìlu Benin,China,Ghana,India,Togo, àtiUnited Kingdom.[10][11][12][13]
Babájídé Sanwóolú ni gómìnà ìpínlè Èkó.
- ↑SeeList of Governors of Lagos State for a list of prior governors
- ↑"Lagos State - Population".Archived from the original on 2008-02-25. Retrieved2009-07-22.
- ↑3.03.1"C-GIDD (Canback Global Income Distribution Database)". Canback Dangel. Retrieved2008-08-20.
- ↑Onyeakagbu, Adaobi."See how all the 36 Nigerian states got their names".Pulse.ng. Archived fromthe original on 11 August 2022. Retrieved25 December 2021.
- ↑"This is how the 36 states were created".Pulse.ng. 24 October 2017. Retrieved22 December 2021.
- ↑"Lagos | Nigeria Education".nigeria-education.org. Retrieved2020-05-30.
- ↑Amao, J. O.; Oluwatayo, I. B.; Osuntope, F. K. (24 Oct 2017). "Economics of Fish Demands in Lagos State, Nigeria". Journal of Human Ecology 19 (1): 25–30. doi:10.1080/09709274.2006.11905853. https://www.tandfonline.com/doi/abs/10.1080/09709274.2006.11905853?journalCode=rhue20. Retrieved 2 January 2022.
- ↑Olufowobi, Sesan (10 September 2018)."Sea cow rescued in Lagos".The Punch. Retrieved2 January 2022.
- ↑"Lagos Population 2022 (Demographics, Maps, Graphs)".worldpopulationreview.com. Retrieved2022-07-23.
- ↑Adeshokan, Oluwatosin (10 January 2020)."The last French speakers in Lagos".Mail & Guardian. Retrieved3 January 2022.
- ↑"In Nigeria, Chinatown Vendors Struggle For Profits".NPR. Retrieved3 January 2022.
- ↑Fawehinmi, Yolanthe (26 October 2021). "Meet the British-Nigerians swapping London for 'Africa's Silicon Valley'". https://www.telegraph.co.uk/family/life/meet-british-nigerians-swapping-london-africas-silicon-valley/.
- ↑Ndukwe, Ijeoma."'Everyone is hustling here': The Lebanese of Nigeria".Al Jazeera. Retrieved2 January 2022.
|
---|
|
Administrative divisions | | |
---|
Àwọn Agbègbè Ìjọba Ìbílẹ̀ | |
---|